Ọlọ́run rò pé a gbọdọ̀ kọ́ nípa ètò àti ìkójọ láti ara ètò pípé tí Ó gbé kalẹ̀ nígbà ayé e Mósè, fún ànfààní àwọn ọmọ Ísírẹ́lì.- Testimonies,vol.1, p.653. IIO 73.3