Níbi ìgbọ́wọ́ lé lórí àwọn méjìlá ni ìgbésẹ̀ àkọ́kọ́ ti wáyé nínú ìjọ kíkójọ pé lẹ́yìn tí Jésù bá gòkè lọ sí ọ̀run wọn yóò lè tẹ̀síwájú nínú iṣẹ́ ẹ Rẹ̀ ní ayé.- The Acts of The Apostles, p.18. IIO 73.4